﴿آمَنَ الرَّسُولُ بِمَا أُنزِلَ إِلَيْهِ مِن رَّبِّهِ وَالْمُؤْمِنُونَ كُلٌّ آمَنَ بِاللَّهِ وَمَلآئِكَتِهِ وَكُتُبِهِ وَرُسُلِهِ لاَ نُفَرِّقُ بَيْنَ أَحَدٍ مِّن رُّسُلِهِ وَقَالُواْ سَمِعْنَا وَأَطَعْنَا غُفْرَانَكَ رَبَّنَا وَإِلَيْكَ الْمَصِيرُ* لاَ يُكَلِّفُ اللَّهُ نَفْساً إِلاَّ وُسْعَهَا لَهَا مَا كَسَبَتْ وَعَلَيْهَا مَا اكْتَسَبَتْ رَبَّنَا لاَ تُؤَاخِذْنَا إِن نَّسِينَا أَوْ أَخْطَأْنَا رَبَّنَا وَلاَ تَحْمِلْ عَلَيْنَا إِصْراً كَمَا حَمَلْتَهُ عَلَى الَّذِينَ مِن قَبْلِنَا رَبَّنَا وَلاَ تُحَمِّلْنَا مَا لاَ طَاقَةَ لَنَا بِهِ وَاعْفُ عَنَّا وَاغْفِرْ لَنَا وَارْحَمْنَآ أَنتَ مَوْلاَنَا فَانصُرْنَا عَلَى الْقَوْمِ الْكَافِرِينَ﴾.
Ojise nigbagbo si ohun ti won sokale fun un lati odo Olohun Oba re, ati pe awon olugbagbo ododo naa nigbagbo si ohun ti won sokale fun ojise, gbogbo won ni won ni igbagbo ninu Olohun ati awon malaika Re, ati awon tira Re, ati awon ojise Re, a o nii se iyato Kankan ninu awon ojise Re, awon olugbagbo ododo yio so wipe a gbo ti E Oluwa wa, a si tele ase Re, fori ese wa jin wa, Olohun wa, odo Re naa ni ifi abo si. Olohun ko la nkankan bo emi kan lorun ayafi ohun ti o ni agbara re, ti emi ni yio maa je ise rere toba se, oun naa lo ni ohun aburu ti o ba se, Olohun Oba ma se fi iya je wa nigba ti a ba gbagbe nkan abi ti a ba se asise, Olohun Oba wa, ma gbe eru ese le wa lori, gege bi O se gbe e le awon ti o ti saaju wa lori, Olohun ma se di eru ti a o nii le gbe ru wa, ni amojukuro fun wa, se aforiji ese wa, si ke wa, Iwo ni Oluwa wa, je ki a bori gbogbo ijo keferi
Gbọ́ · Ohùn Hamad al-Duraiham